Ezekiel 20:5
5
kí ó sì sọ fún wọn pé: ‘Báyìí ní
Olúwa
Olódùmarè wí: Ní ọjọ́ tí mo yàn Israẹli, mo gbé ọwọ́ mi sókè nínú ìbúra sí àwọn ọmọ ilé Jakọbu, mo sì fi ara mi hàn wọn ní Ejibiti, mo gbé ọwọ́ mi sókè nínú ẹ̀jẹ́ wí pé, “Èmi ni
Olúwa
Ọlọ́run yín.”
Copyright information for
YorBMYO